Ojukaye TV

Ojukaye TV OJUKAYE TV is a Nigerian digital media platform delivering entertainment, culture, news, interviews, comedy, and inspiring stories across the world.
(7)

🔔 Awọn ilé iṣẹ́ ọlọpaa ti pe Senator Fadahunsi lori ọrọ to sọ wípé ó ń gbà àwọn ènìyàn  ní ìmọ̀ràn lati "pa awọn ọmọ ẹgb...
13/08/2026

🔔 Awọn ilé iṣẹ́ ọlọpaa ti pe Senator Fadahunsi lori ọrọ to sọ wípé ó ń gbà àwọn ènìyàn ní ìmọ̀ràn lati "pa awọn ọmọ ẹgbẹ Accord" ṣaaju idibo gomina ipinle Osun.
Wọn ní kó wá sọ nkan tó rí nínú ọ̀bẹ tó fi wá irú sì ọwọ́
Ṣáájú ni Senator Fadunsi tí so ni ibo ìpolongo ibo egbe APC fún idibo Gomina losun pé kí wọ́n máa paa gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ accord tiwọn ba tiri nínú fídíò kan tó gbà ojú ayélujára.

Ẹ ka ẹkùnrẹ́rẹ́ ìròyìn yí ni WhatsApp Channel Ojukaye Tv 👇👇👇👇👇👇🤣 https://whatsapp.com/channel/0029VbCAIBdF1YlZHekzMo2g

11/08/2026

Dẹ́kun gbígbẹ́kẹ̀lé àkókò tó dára jù lọ.

Ọkọ̀ HILUX TÍ ÒÒNÌ ÒRÌṢÀ FÙN CHIEF SUNDAY IGBOHO TÍ TÈ BÀǸDÌ FÚN ÌRÙ Ẹ̀KÙN​Ẹ Ṣé PÚPỌ̀ CHIEF SUNDAY IGBOHO​Ẹ Ṣé PÚPỌ̀ Àr...
11/08/2026

Ọkọ̀ HILUX TÍ ÒÒNÌ ÒRÌṢÀ FÙN CHIEF SUNDAY IGBOHO TÍ TÈ BÀǸDÌ FÚN ÌRÙ Ẹ̀KÙN
​Ẹ Ṣé PÚPỌ̀ CHIEF SUNDAY IGBOHO
​Ẹ Ṣé PÚPỌ̀ Àrólé Odùduwà Fún Ààbọ̀ ILẸ̀ YORÙBÁ

Naijiria ni orilẹ-ede ti o ni awọn eniyan púpọ̀ julọ ni ilẹ Afirika ati eyi ti o wa ni ipo kẹsan-an laarin awọn orilẹ-ed...
10/08/2026

Naijiria ni orilẹ-ede ti o ni awọn eniyan púpọ̀ julọ ni ilẹ Afirika ati eyi ti o wa ni ipo kẹsan-an laarin awọn orilẹ-ede ti o n lo intanẹẹti julọ pẹlu awọn eniyan ti o pọ̀ to 108 million ti wọn wa lori ẹrọ ayelujara.
​Larin oṣu mẹfa akọkọ ọdun 2026 nikan, MTN ti ri nkan bii 3 trillion Naira ($2.993 trillion) lowo awọn ọmọ Naijiria.
​Awon eleyi pẹlu:
​1.7 trillion Naira lati ẹrọ data.
​897.1 billion Naira lati ipe foonu.
​112.7 billion Naira lati itẹwe ranṣẹ (SMS).
​Lojoojumọ ni awọn ọmọ Naijiria n lo 45,800 Terabytes ti data. A tiledẹ sọ pe o jẹiṣiro ti o din ku gẹgẹ bii 200 Naira fun Gigabyte kan, awọn ọmọ Naijiria n na 9.8 billion Naira ni ojojumọ lori data lori ayelujara nikan. Eyi ko tilẹ pẹlu money ti wọn n na lori ipe foonu, itẹwe ranṣẹ tabi awọn owo miiran.
​Ife-inú-jẹ patapata ni pe orilẹ-ede bii Naijiria kò ni ilé-iṣẹ ibaraẹnisọrọ ti orilẹ-ede tirẹ lati mu ki owo yi duro si inu orilẹ-ede na.
​Dipo iyẹn, awọn ilé-iṣẹ ti ajeji bii MTN ati Airtel n gba awọn billions ti Naira kuro ni ojojumọ lakoko ti awọn olori Naijiria ko ṣe nkan kankan. Ẹnikẹni ti o ba ni ọpọlọ yoo mọ pe eyi kò tọ rara.

Ẹni ọdún Merindinlogorun ni mama yí, mama yí si wa, Ǹjẹ́ Ẹyin Mọ̀ Wọ́n? Oya ẹjẹ ká bá wọn yo, pẹ̀lú orúkọ wọn.
07/08/2026

Ẹni ọdún Merindinlogorun ni mama yí, mama yí si wa, Ǹjẹ́ Ẹyin Mọ̀ Wọ́n? Oya ẹjẹ ká bá wọn yo, pẹ̀lú orúkọ wọn.

06/08/2026

GANI ADAMS tio Je Are onakakanfo ilé Yoruba sọ̀rọ̀, lórí ìjà tí ó n wáyé láàárín Àwọn Àti Oloye Sunday Igboho lórí Irú Ẹkùn.

Ìròyìn Pàtàkì: Oloye Sunday Igboho ti kéde ètò láti ṣe àpéjọpọ̀ lórí ọ̀rọ̀ ààbò, èyí tí yóò kó gbogbo àwọn ọba ilẹ̀ Yorù...
05/08/2026

Ìròyìn Pàtàkì: Oloye Sunday Igboho ti kéde ètò láti ṣe àpéjọpọ̀ lórí ọ̀rọ̀ ààbò, èyí tí yóò kó gbogbo àwọn ọba ilẹ̀ Yorùbá papọ̀ .

Gẹ́gẹ́ bí Oloye Igboho ṣe sọ, òun yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní fi àwọn lẹ́tà ìpè ránṣẹ́ sí gbogbo àwọn ọba ní agbègbè Gúúsù-Ìwọ̀-Oòrùn orílẹ̀-èdè yìí láti wá sí àpéjọpọ̀ ààbò náà. Ó fi ìgbàgbọ́ hàn pé gbogbo àwọn ọba ilẹ̀ Yorùbá yóò kópa nínú ìpàdé náà.

Ó ṣe ìkéde yìí ní àná tíì ṣe ọjọ́ kẹrin oṣù Kẹjọ Ọdún 2026, ní ààfin ọba Ogunwusi Eniitan Ojaja 11 Ilé Oodua lẹ́yìn tí Arole Oodua ti fọwọ́ sí àti ṣètìlẹ́yìn fún ètò ààbò rẹ̀ tí a mọ̀ sí 'Iru Ekun Security Network' pẹ̀lú ẹ̀bùn owó tí ó tó ọgọ́rùn-ún mílíọ̀nù náírà (₦100 million) àti ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ Toyota Hilux kan.

05/08/2026
05/08/2026

Ẹ sùn me yín díẹ̀, Ẹ ó jẹ Governor rí,

Ṣé ẹyin ti je Governor rí?
To bá jẹ Ẹyin ni, Kini ẹ máa ṣe?

Address

Ibadan

Website

Alerts

Be the first to know and let us send you an email when Ojukaye TV posts news and promotions. Your email address will not be used for any other purpose, and you can unsubscribe at any time.

Shortcuts

Share