25/11/2025
"Eyi ti o gbà talenti kan si wá, o ni, Oluwa, mo mọ̀ ọ pe onroro enia ni iwọ iṣe, iwọ nkore nibiti iwọ kò gbe funrugbin si, iwọ si nṣà nibiti iwọ kò fẹ́ka si: Emi si bẹ̀ru, mo si lọ pa talenti rẹ mọ́ ninu ilẹ: wo o, nkan rẹ niyi. Oluwa rẹ̀ si dahùn o wi fun u pe, Iwọ ọmọ-ọdọ buburu ati onilọra, iwọ mọ̀ pe emi nkore nibiti emi kò funrugbin si, emi si nṣà nibiti emi kò fẹ́ka si: Nitorina iwọ iba fi owo mi si ọwọ́ awọn ti npowodà, nigbati emi ba de, emi iba si gbà nkan mi pẹlu elé. Nitorina ẹ gbà talenti na li ọwọ́ rẹ̀, ẹ si fifun ẹniti o ni talenti mẹwa." *¹
"Nitori igbati nwọn mọ̀ Ọlọrun, nwọn kò yìn i logo bi Ọlọrun, bẹ̃ni nwọn kò si dupẹ; ṣugbọn èro ọkàn wọn di asán, a si mu ọkàn òmúgọ wọn ṣókunkun." *²
- *¹ Mat 25:24-28 YBCV, *² Rom 1:21 YBCV
🔥🔥🔥🔥🔥🔥🔥
Ẹ ṣeun púpọ̀ tí ẹ yà sí ìhín yìí.
Jo̧wo̧ mase fi igbala rẹ da ọla.
Bi iwọ kò ba i ti ṣe bẹẹ tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ̀, tete fi aiye rẹ fun Jesu Kristi Oluwa loni yii. Nítorípé, ọla leè pẹ ju fún ọ.
⏪⏪⏪⏪⏩⏩⏩⏩
ᴵˡᵉ ᶦˢᵉ ᶦʳᵃⁿˢᵉ ʸᶦᶦ' ᵏᶦ ᶦ ˢᵉ ᶦᵈᵃˢᶦˡᵉ ᶦʲᵒ ᶠᵘⁿ ᵉˢᶦⁿ' ᵇᶦᵏᵒˢᵉ ᶦᵇᶦᵗᶦ ᵃ ᵗᶦ ⁿᶠᶦ ᶦᶠᵉ ᴼˡᵒʳᵘⁿ ᵍᵇᵉ ᵖᵉˡᵘ ᵃᵗᶦ ˢᵉ ᵃᵐᵒʲᵘᵗᵒ ᵃʷᵒⁿ ᵉⁿᶦʸᵃⁿ ᵗᶦ ᵏᵒ ʳᵒʳᵘⁿ ˡᵃᵗᶦ ᵐᵃᵃ ᵇᵃ ᵍᵇᵉ˙ ᴬʷᵒⁿ ᵉⁿᶦᵗᶦ ᵃʸᵉ' ᴱˢᵘ ᵗᵃᵇᶦ ᵉˢᵉ ⁿᵖᵒⁿ ˡᵒʲᵘ˙
ᴶᵉˢᵘ ᴷʳᶦˢᵗᶦ ᴼˡᵘʷᵃ ⁿᶦ ᴼˡᵘᵍᵇᵃˡᵃ ᵃᵗᶦ ᴼˡᵘʷᵒˢᵃⁿ ʷᵒⁿ' ⁿᶦᵖᵃˢᵉ ᵃʷᵒⁿ ᴼʳᵒ ᴿᵉ ᵇᶦ ᶦʳᵘ ᵉʸᶦ˙
𝙵ú𝚗 à𝚕à𝚢é 𝚝à𝚋í ì𝚋éè𝚛è, ę 𝚙è 𝚝à𝚋í 𝚝ę 𝚊𝚝ę𝚓𝚒șę 𝚢í𝚗 𝚜𝚒:
📱07038226570.
📩 [email protected]
̷є̣ ѕὶ ℓєє̀ кὰη ѕὶ ωα ηί:
IBUDO~ẸRI KRISTI
(ɪʟᴇ ᴍᴀᴀʏᴇ), ABÚLÉ ÒGOBÌ-ỌJÀ,
ʟᴇ̣ʜɪɴ ᴏ̣ɢʙᴀ ʀᴇᴅᴇᴇᴍᴇʀ'ᴤ ᴜɴɪᴠᴇʀᴤɪᴛʏ, ẸDẸ, NI IPINLẸ ỌSUN, NIGERIA.
Olúwa yóò máa bùkún fun yín.