30/12/2025
- Wọn tun ṣọọṣẹ laabi wọn o, Àwọn ajínigbé sekọlu s'ilú Adanla ní Kwara, jí èèyàn mẹ́sàn-án gbé lọ, yìnbọn sekupa ẹnìkan
- Ọgbọn billiọnu naira N30bn ni ijọba apapọ yọnda kiise Àádọta billiọnu naira N50bn fún ìrànlọ́wọ́ lori iṣẹlẹ ibugbamu to waye n'Ibadan - Abẹsinkawọ Makinde lo yannayanna ọrọ bẹẹ
- Haa! awọn agbebọn ji Pasitọ ìjọ Living Faith gbe salọ nipinlẹ Kogi
- Haa! Gbajumọ Akansẹkubiojo nní Anthony Joshua se kongẹ ìjàmbá ọkọ ni Makun, nipinlẹ Ogun, awọn meji mii pàdánù ẹmi wọn
- Iku Gbajumo oserebinrin Allwell Ademola yi bawa lojiji o, ẹ gbọ ohun tawọn eeyan nsọ nipa rẹ
- Àwọn tó gba wèrè mẹ́sìn ló kórìíra àṣà àti ìṣe Yorùbá, àṣà wa ò gbọdọ̀ parun - Àwọn olóyè ìlú Osi lo kìlọ̀ bẹẹ
- Ẹyin Munkan munkan ẹlẹnu arọ ẹ tẹti ẹ gbọ o Òfin tí ìjọba Nàìjíríà fi de ọtí inú ọ̀rá, alafẹnju bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ tó gbẹ̀yìn lọ́dún yii
- Iwọ̀nyí làwọn orí adé ọrùn ilẹkẹ àti olóṣèlú tó dágbére f'aye ní Naijiria àti nilẹ adulawọ l'Afrika lọ́dún 2025
- Ganusi, Kundus, Opueh, If E reach ur turn, Atasa àtàwọn ọ̀rọ̀ ìgboro míì tó gba igboro kan ní Naijiria lọ́dún 2025 ni wọnyi
ANTHONY JOSHUA SE KONGE IJAMBA OKO NI MAKUN, NIPINLE OGUN, AWON MEJI MII PADANU EMI WON- Wọn tun ṣọọṣẹ laabi wọn o, Àwọn ajínigbé sekọlu s'ilú Adanla ní Kwar...